سورة إبراهيم باليوربا

  1. استمع للسورة
  2. سور أخرى
  3. ترجمة السورة
القرآن الكريم | ترجمة معاني القرآن | اللغة اليوربا | سورة إبراهيم | Ibrahim - عدد آياتها 52 - رقم السورة في المصحف: 14 - معنى السورة بالإنجليزية: Abraham.

الر ۚ كِتَابٌ أَنزَلْنَاهُ إِلَيْكَ لِتُخْرِجَ النَّاسَ مِنَ الظُّلُمَاتِ إِلَى النُّورِ بِإِذْنِ رَبِّهِمْ إِلَىٰ صِرَاطِ الْعَزِيزِ الْحَمِيدِ(1)

’Alif lam ro. (Eyi ni) Tira kan ti A sokale fun o nitori ki o le mu awon eniyan kuro lati inu awon okunkun wa sinu imole pelu iyonda Oluwa won. (Won yo si bo) si ona Alagbara, Olope (ti ope to si)

اللَّهِ الَّذِي لَهُ مَا فِي السَّمَاوَاتِ وَمَا فِي الْأَرْضِ ۗ وَوَيْلٌ لِّلْكَافِرِينَ مِنْ عَذَابٍ شَدِيدٍ(2)

Allahu, Eni ti O ni ohunkohun t’o wa ninu awon sanmo ati ohunkohun t’o wa ninu ile. Egbe ni fun awon alaigbagbo nibi iya lile

الَّذِينَ يَسْتَحِبُّونَ الْحَيَاةَ الدُّنْيَا عَلَى الْآخِرَةِ وَيَصُدُّونَ عَن سَبِيلِ اللَّهِ وَيَبْغُونَهَا عِوَجًا ۚ أُولَٰئِكَ فِي ضَلَالٍ بَعِيدٍ(3)

Awon t’o n feran isemi aye ju torun, ti won n seri awon eniyan kuro loju ona (esin) Allahu, won si n fe ko wo; awon wonyen wa ninu isina t’o jinna

وَمَا أَرْسَلْنَا مِن رَّسُولٍ إِلَّا بِلِسَانِ قَوْمِهِ لِيُبَيِّنَ لَهُمْ ۖ فَيُضِلُّ اللَّهُ مَن يَشَاءُ وَيَهْدِي مَن يَشَاءُ ۚ وَهُوَ الْعَزِيزُ الْحَكِيمُ(4)

A o ran Ojise kan nise afi pelu ede ijo re1 nitori ki o le salaye (esin) fun won. Nigba naa, Allahu yoo si enikeni ti O ba fe lona. O si maa to enikeni ti O ba fe sona; Oun ni Alagbara, Ologbon

وَلَقَدْ أَرْسَلْنَا مُوسَىٰ بِآيَاتِنَا أَنْ أَخْرِجْ قَوْمَكَ مِنَ الظُّلُمَاتِ إِلَى النُّورِ وَذَكِّرْهُم بِأَيَّامِ اللَّهِ ۚ إِنَّ فِي ذَٰلِكَ لَآيَاتٍ لِّكُلِّ صَبَّارٍ شَكُورٍ(5)

A kuku fi awon ayah Wa ran (Anabi) Musa nise pe: “Mu ijo re kuro lati inu awon okunkun bo sinu imole. Ki o si ran won leti awon idera Allahu (lori won).” Dajudaju awon ami wa ninu iyen fun gbogbo onisuuru, oludupe

وَإِذْ قَالَ مُوسَىٰ لِقَوْمِهِ اذْكُرُوا نِعْمَةَ اللَّهِ عَلَيْكُمْ إِذْ أَنجَاكُم مِّنْ آلِ فِرْعَوْنَ يَسُومُونَكُمْ سُوءَ الْعَذَابِ وَيُذَبِّحُونَ أَبْنَاءَكُمْ وَيَسْتَحْيُونَ نِسَاءَكُمْ ۚ وَفِي ذَٰلِكُم بَلَاءٌ مِّن رَّبِّكُمْ عَظِيمٌ(6)

(Ranti) nigba ti (Anabi) Musa so fun ijo re pe e ranti ike Allahu lori yin nigba ti O gba yin la lowo awon eniyan Fir‘aon, ti won n fi iya buruku je yin; won n dunnbu awon omokunrin yin, won si n da awon omobinrin yin si. Adanwo nla wa ninu iyen lati odo Oluwa yin

وَإِذْ تَأَذَّنَ رَبُّكُمْ لَئِن شَكَرْتُمْ لَأَزِيدَنَّكُمْ ۖ وَلَئِن كَفَرْتُمْ إِنَّ عَذَابِي لَشَدِيدٌ(7)

(E ranti) nigba ti Oluwa Eledaa yin so o di mimo (fun yin pe): "Dajudaju ti e ba dupe, Emi yoo salekun fun yin. Dajudaju ti e ba si saimoore, dajudaju iya Mi ma le

وَقَالَ مُوسَىٰ إِن تَكْفُرُوا أَنتُمْ وَمَن فِي الْأَرْضِ جَمِيعًا فَإِنَّ اللَّهَ لَغَنِيٌّ حَمِيدٌ(8)

(Anabi) Musa so pe: "Ti e ba saimoore, eyin ati awon t’o n be lori ile aye patapata, dajudaju Allahu ni Oloro, Olope

أَلَمْ يَأْتِكُمْ نَبَأُ الَّذِينَ مِن قَبْلِكُمْ قَوْمِ نُوحٍ وَعَادٍ وَثَمُودَ ۛ وَالَّذِينَ مِن بَعْدِهِمْ ۛ لَا يَعْلَمُهُمْ إِلَّا اللَّهُ ۚ جَاءَتْهُمْ رُسُلُهُم بِالْبَيِّنَاتِ فَرَدُّوا أَيْدِيَهُمْ فِي أَفْوَاهِهِمْ وَقَالُوا إِنَّا كَفَرْنَا بِمَا أُرْسِلْتُم بِهِ وَإِنَّا لَفِي شَكٍّ مِّمَّا تَدْعُونَنَا إِلَيْهِ مُرِيبٍ(9)

Se iro awon t’o siwaju yin ko ti i de ba yin ni? Ijo (Anabi) Nuh, ijo ‘Ad, ijo Thamud ati awon t’o wa leyin won; ko si eni ti o mo won afi Allahu. Awon Ojise won mu awon eri t’o yanju wa ba won. Nigba naa, won ti owo won bo enu won (ni ti ibinu), won si wi pe: "Dajudaju awa sai gbagbo ninu nnkan ti Won fi ran yin nise. Ati pe dajudaju awa wa ninu iyemeji t’o gbopon nipa ohun ti e n pe wa si

۞ قَالَتْ رُسُلُهُمْ أَفِي اللَّهِ شَكٌّ فَاطِرِ السَّمَاوَاتِ وَالْأَرْضِ ۖ يَدْعُوكُمْ لِيَغْفِرَ لَكُم مِّن ذُنُوبِكُمْ وَيُؤَخِّرَكُمْ إِلَىٰ أَجَلٍ مُّسَمًّى ۚ قَالُوا إِنْ أَنتُمْ إِلَّا بَشَرٌ مِّثْلُنَا تُرِيدُونَ أَن تَصُدُّونَا عَمَّا كَانَ يَعْبُدُ آبَاؤُنَا فَأْتُونَا بِسُلْطَانٍ مُّبِينٍ(10)

Awon Ojise won so pe: “Se iyemeji kan n be nibi (bibe) Allahu, Olupileda awon sanmo ati ile? O n pe yin nitori ki O le fori awon ese yin jin yin ati nitori ki O le lo yin lara di gbedeke akoko kan.” Won wi pe: “Eyin ko je kini kan tayo abara bi iru wa. Eyin si fe se wa lori kuro nibi nnkan ti awon baba wa n josin fun. Nitori naa, e fun wa ni eri ponnbele.”

قَالَتْ لَهُمْ رُسُلُهُمْ إِن نَّحْنُ إِلَّا بَشَرٌ مِّثْلُكُمْ وَلَٰكِنَّ اللَّهَ يَمُنُّ عَلَىٰ مَن يَشَاءُ مِنْ عِبَادِهِ ۖ وَمَا كَانَ لَنَا أَن نَّأْتِيَكُم بِسُلْطَانٍ إِلَّا بِإِذْنِ اللَّهِ ۚ وَعَلَى اللَّهِ فَلْيَتَوَكَّلِ الْمُؤْمِنُونَ(11)

Awon Ojise won so fun won pe: “Awa ko je kini kan bi ko se abara bi iru yin. Sugbon Allahu n soore fun eni ti O ba fe ninu awon erusin Re. Ko si letoo fun wa lati fun yin ni eri kan afi pelu iyonda Allahu. Ati pe, Allahu ni ki awon onigbagbo ododo gbarale

وَمَا لَنَا أَلَّا نَتَوَكَّلَ عَلَى اللَّهِ وَقَدْ هَدَانَا سُبُلَنَا ۚ وَلَنَصْبِرَنَّ عَلَىٰ مَا آذَيْتُمُونَا ۚ وَعَلَى اللَّهِ فَلْيَتَوَكَّلِ الْمُتَوَكِّلُونَ(12)

Ki ni o maa se wa ti a o nii gbarale Allahu, O kuku ti fi awon ona wa mo wa. Dajudaju a maa se suuru lori ohun ti e ba fi ko inira ba wa. Allahu si ni ki awon olugbarale gbarale.”

وَقَالَ الَّذِينَ كَفَرُوا لِرُسُلِهِمْ لَنُخْرِجَنَّكُم مِّنْ أَرْضِنَا أَوْ لَتَعُودُنَّ فِي مِلَّتِنَا ۖ فَأَوْحَىٰ إِلَيْهِمْ رَبُّهُمْ لَنُهْلِكَنَّ الظَّالِمِينَ(13)

Awon t’o sai gbagbo wi fun awon Ojise won pe: “Dajudaju awa yoo le yin jade kuro lori ile wa tabi ki e kuku pada sinu esin wa.” Nigba naa, Oluwa won fi imisi ranse si won pe: “Dajudaju A maa pa awon alabosi run

وَلَنُسْكِنَنَّكُمُ الْأَرْضَ مِن بَعْدِهِمْ ۚ ذَٰلِكَ لِمَنْ خَافَ مَقَامِي وَخَافَ وَعِيدِ(14)

Dajudaju A si maa fun yin ni ibugbe lori ile leyin won. ” Iyen wa fun eni ti o ba paya iduro (niwaju) Mi, ti o tun paya ileri Mi

وَاسْتَفْتَحُوا وَخَابَ كُلُّ جَبَّارٍ عَنِيدٍ(15)

Won si toro aranse (Allahu lori ijo won). Gbogbo alafojudi, olorikunkun si padanu

مِّن وَرَائِهِ جَهَنَّمُ وَيُسْقَىٰ مِن مَّاءٍ صَدِيدٍ(16)

Ina Jahanamo n be leyin (iparun) re; A o si maa fun un ni omi awoyunweje mu

يَتَجَرَّعُهُ وَلَا يَكَادُ يُسِيغُهُ وَيَأْتِيهِ الْمَوْتُ مِن كُلِّ مَكَانٍ وَمَا هُوَ بِمَيِّتٍ ۖ وَمِن وَرَائِهِ عَذَابٌ غَلِيظٌ(17)

O maa sare mu un diedie, ko si nii fee le gbe e mi. (Inira) iku yo si maa yo si i ni gbogbo aye, sibe ko nii ku. Iya t’o nipon tun wa fun un leyin re

مَّثَلُ الَّذِينَ كَفَرُوا بِرَبِّهِمْ ۖ أَعْمَالُهُمْ كَرَمَادٍ اشْتَدَّتْ بِهِ الرِّيحُ فِي يَوْمٍ عَاصِفٍ ۖ لَّا يَقْدِرُونَ مِمَّا كَسَبُوا عَلَىٰ شَيْءٍ ۚ ذَٰلِكَ هُوَ الضَّلَالُ الْبَعِيدُ(18)

Afiwe awon t’o sai gbagbo ninu Oluwa won: awon ise won da bi eeru ti ategun fe danu patapata ni ojo iji ategun. Won ko ni agbara kan lori ohun ti won se nise. Iyen ni isina t’o jinna

أَلَمْ تَرَ أَنَّ اللَّهَ خَلَقَ السَّمَاوَاتِ وَالْأَرْضَ بِالْحَقِّ ۚ إِن يَشَأْ يُذْهِبْكُمْ وَيَأْتِ بِخَلْقٍ جَدِيدٍ(19)

Se o o ri i pe dajudaju Allahu l’O seda awon sanmo ati ile pelu ododo? Ti O ba fe, O maa ko yin kuro. O si maa mu eda titun wa

وَمَا ذَٰلِكَ عَلَى اللَّهِ بِعَزِيزٍ(20)

Iyen ko si le da Allahu lagara

وَبَرَزُوا لِلَّهِ جَمِيعًا فَقَالَ الضُّعَفَاءُ لِلَّذِينَ اسْتَكْبَرُوا إِنَّا كُنَّا لَكُمْ تَبَعًا فَهَلْ أَنتُم مُّغْنُونَ عَنَّا مِنْ عَذَابِ اللَّهِ مِن شَيْءٍ ۚ قَالُوا لَوْ هَدَانَا اللَّهُ لَهَدَيْنَاكُمْ ۖ سَوَاءٌ عَلَيْنَا أَجَزِعْنَا أَمْ صَبَرْنَا مَا لَنَا مِن مَّحِيصٍ(21)

Gbogbo eda si maa jade sodo Allahu (lojo Ajinde). Nigba naa, awon alailagbara yoo wi fun awon t’o segberaga pe: “Dajudaju awa je omoleyin fun yin, nje eyin le gbe nnkan kan kuro fun wa ninu iya Allahu?” Won yoo wi pe: “Ti o ba je pe Allahu to wa sona ni, awa iba to yin sona. Bakan naa si ni fun wa, yala a kaya soke tabi a satemora (iya); ko si ibusasi kan fun wa.”

وَقَالَ الشَّيْطَانُ لَمَّا قُضِيَ الْأَمْرُ إِنَّ اللَّهَ وَعَدَكُمْ وَعْدَ الْحَقِّ وَوَعَدتُّكُمْ فَأَخْلَفْتُكُمْ ۖ وَمَا كَانَ لِيَ عَلَيْكُم مِّن سُلْطَانٍ إِلَّا أَن دَعَوْتُكُمْ فَاسْتَجَبْتُمْ لِي ۖ فَلَا تَلُومُونِي وَلُومُوا أَنفُسَكُم ۖ مَّا أَنَا بِمُصْرِخِكُمْ وَمَا أَنتُم بِمُصْرِخِيَّ ۖ إِنِّي كَفَرْتُ بِمَا أَشْرَكْتُمُونِ مِن قَبْلُ ۗ إِنَّ الظَّالِمِينَ لَهُمْ عَذَابٌ أَلِيمٌ(22)

Esu yo si wi nigba ti A ba sedajo (eda) tan, pe: “Dajudaju Allahu se adehun fun yin ni adehun ododo. Emi naa se adehun fun yin. Mo si yapa adehun ti mo se fun yin. Emi ko si ni agbara kan lori yin bi ko se pe mo pe yin e si jepe mi. Nitori naa, e ma se bu mi; ara yin ni ki e bu. Emi ko le ran yin lowo (nibi iya), Eyin naa ko si le ran mi lowo (nibi iya). Dajudaju emi ti lodi si ohun ti e fi so mi di akegbe Allahu siwaju.” Dajudaju awon alabosi, iya eleta-elero wa fun won

وَأُدْخِلَ الَّذِينَ آمَنُوا وَعَمِلُوا الصَّالِحَاتِ جَنَّاتٍ تَجْرِي مِن تَحْتِهَا الْأَنْهَارُ خَالِدِينَ فِيهَا بِإِذْنِ رَبِّهِمْ ۖ تَحِيَّتُهُمْ فِيهَا سَلَامٌ(23)

Won si maa mu awon t’o gbagbo ni ododo, ti won si se awon ise rere wo inu awon Ogba Idera, eyi ti awon odo n san ni isale re. Olusegbere ni won ninu re pelu ase Oluwa won. Ikini won ninu re ni ‘alaafia’

أَلَمْ تَرَ كَيْفَ ضَرَبَ اللَّهُ مَثَلًا كَلِمَةً طَيِّبَةً كَشَجَرَةٍ طَيِّبَةٍ أَصْلُهَا ثَابِتٌ وَفَرْعُهَا فِي السَّمَاءِ(24)

Se o o ri bi Allahu ti sakawe oro daadaa pelu igi daadaa, ti gbongbo re fidi mule sinsin, ti eka re si wa ninu sanmo

تُؤْتِي أُكُلَهَا كُلَّ حِينٍ بِإِذْنِ رَبِّهَا ۗ وَيَضْرِبُ اللَّهُ الْأَمْثَالَ لِلنَّاسِ لَعَلَّهُمْ يَتَذَكَّرُونَ(25)

to si n so eso (jije) re ni gbogbo igba pelu iyonda Oluwa re? Allahu n fun awon eniyan ni awon akawe nitori ki won le lo iranti

وَمَثَلُ كَلِمَةٍ خَبِيثَةٍ كَشَجَرَةٍ خَبِيثَةٍ اجْتُثَّتْ مِن فَوْقِ الْأَرْضِ مَا لَهَا مِن قَرَارٍ(26)

Akawe oro ti ko dara si da bi igi ti ko dara, ti won fa tu lati oke lori ile, ti ko si ni aye kan lori ile

يُثَبِّتُ اللَّهُ الَّذِينَ آمَنُوا بِالْقَوْلِ الثَّابِتِ فِي الْحَيَاةِ الدُّنْيَا وَفِي الْآخِرَةِ ۖ وَيُضِلُّ اللَّهُ الظَّالِمِينَ ۚ وَيَفْعَلُ اللَّهُ مَا يَشَاءُ(27)

Allahu yoo maa fi awon t’o gbagbo ni ododo rinle pelu oro t’o rinle ninu isemi aye ati ni Ojo Ikeyin. O si maa si awon alabosi lona. Ati pe Allahu n se ohun ti O ba fe

۞ أَلَمْ تَرَ إِلَى الَّذِينَ بَدَّلُوا نِعْمَتَ اللَّهِ كُفْرًا وَأَحَلُّوا قَوْمَهُمْ دَارَ الْبَوَارِ(28)

Se o o ri awon t’o yi idera Allahu pada si aigbagbo, ti won si mu ijo won gunle si ile iparun

جَهَنَّمَ يَصْلَوْنَهَا ۖ وَبِئْسَ الْقَرَارُ(29)

Ina Jahanamo ni won yoo gunle si; ibugbe naa si buru

وَجَعَلُوا لِلَّهِ أَندَادًا لِّيُضِلُّوا عَن سَبِيلِهِ ۗ قُلْ تَمَتَّعُوا فَإِنَّ مَصِيرَكُمْ إِلَى النَّارِ(30)

Won so (awon kan di) akegbe fun Allahu nitori ki won le seri awon eniyan kuro ninu esin Re. So pe: “E maa gbadun nso, nitori pe dajudaju abo yin ni Ina.”

قُل لِّعِبَادِيَ الَّذِينَ آمَنُوا يُقِيمُوا الصَّلَاةَ وَيُنفِقُوا مِمَّا رَزَقْنَاهُمْ سِرًّا وَعَلَانِيَةً مِّن قَبْلِ أَن يَأْتِيَ يَوْمٌ لَّا بَيْعٌ فِيهِ وَلَا خِلَالٌ(31)

So fun awon erusin Mi pe ki won kirun, ki won si na ninu ohun ti A pese fun won ni ikoko ati ni gbangba siwaju ki ojo kan to de, ti ko nii si tita-rira kan ati yiyan ore kan ninu re

اللَّهُ الَّذِي خَلَقَ السَّمَاوَاتِ وَالْأَرْضَ وَأَنزَلَ مِنَ السَّمَاءِ مَاءً فَأَخْرَجَ بِهِ مِنَ الثَّمَرَاتِ رِزْقًا لَّكُمْ ۖ وَسَخَّرَ لَكُمُ الْفُلْكَ لِتَجْرِيَ فِي الْبَحْرِ بِأَمْرِهِ ۖ وَسَخَّرَ لَكُمُ الْأَنْهَارَ(32)

Allahu ni Eni ti O seda awon sanmo ati ile. O n so omi kale lati sanmo. O si fi n mu awon eso jade; (o je) arisiki fun yin. O si ro oko oju-omi fun yin ki o le rin loju omi pelu ase Re. O tun ro awon odo fun yin

وَسَخَّرَ لَكُمُ الشَّمْسَ وَالْقَمَرَ دَائِبَيْنِ ۖ وَسَخَّرَ لَكُمُ اللَّيْلَ وَالنَّهَارَ(33)

O ro oorun ati osupa fun yin, ti mejeeji n rin lai sinmi. O tun ro oru ati osan fun yin

وَآتَاكُم مِّن كُلِّ مَا سَأَلْتُمُوهُ ۚ وَإِن تَعُدُّوا نِعْمَتَ اللَّهِ لَا تُحْصُوهَا ۗ إِنَّ الْإِنسَانَ لَظَلُومٌ كَفَّارٌ(34)

Ati pe O n fun yin ninu gbogbo nnkan ti e toro lodo Re. Ti e ba se onka idera Allahu, e ko le ka a tan. Dajudaju eniyan ni alabosi alaimoore

وَإِذْ قَالَ إِبْرَاهِيمُ رَبِّ اجْعَلْ هَٰذَا الْبَلَدَ آمِنًا وَاجْنُبْنِي وَبَنِيَّ أَن نَّعْبُدَ الْأَصْنَامَ(35)

(Ranti) nigba ti (Anabi) ’Ibrohim so pe: "Oluwa mi, se ilu yii ni ilu ifayabale. Ki O si mu emi ati awon omo mi jinna si jijosin fun awon orisa

رَبِّ إِنَّهُنَّ أَضْلَلْنَ كَثِيرًا مِّنَ النَّاسِ ۖ فَمَن تَبِعَنِي فَإِنَّهُ مِنِّي ۖ وَمَنْ عَصَانِي فَإِنَّكَ غَفُورٌ رَّحِيمٌ(36)

Oluwa mi, dajudaju awon orisa ti ko opolopo ninu awon eniyan sonu. Nitori naa, enikeni ti o ba tele mi, dajudaju oun ni eni mi. Enikeni ti o ba si yapa mi, dajudaju Iwo ni Alaforijin, Asake

رَّبَّنَا إِنِّي أَسْكَنتُ مِن ذُرِّيَّتِي بِوَادٍ غَيْرِ ذِي زَرْعٍ عِندَ بَيْتِكَ الْمُحَرَّمِ رَبَّنَا لِيُقِيمُوا الصَّلَاةَ فَاجْعَلْ أَفْئِدَةً مِّنَ النَّاسِ تَهْوِي إِلَيْهِمْ وَارْزُقْهُم مِّنَ الثَّمَرَاتِ لَعَلَّهُمْ يَشْكُرُونَ(37)

Oluwa wa, dajudaju emi wa ibugbe fun aromodomo mi si ile afonifoji, ile ti ko ni eso, nitosi Ile Re Olowo. Oluwa wa, nitori ki won le kirun ni. Nitori naa, je ki okan awon eniyan fa sodo won. Ki O si pese awon eso fun won nitori ki won le dupe (fun O)

رَبَّنَا إِنَّكَ تَعْلَمُ مَا نُخْفِي وَمَا نُعْلِنُ ۗ وَمَا يَخْفَىٰ عَلَى اللَّهِ مِن شَيْءٍ فِي الْأَرْضِ وَلَا فِي السَّمَاءِ(38)

Oluwa wa, dajudaju Iwo l’O mo ohun ti a n fi pamo ati ohun ti a n se afihan re. Ko si si kini kan ninu ile ati ninu sanmo t’o pamo fun Allahu

الْحَمْدُ لِلَّهِ الَّذِي وَهَبَ لِي عَلَى الْكِبَرِ إِسْمَاعِيلَ وَإِسْحَاقَ ۚ إِنَّ رَبِّي لَسَمِيعُ الدُّعَاءِ(39)

Gbogbo ope n je ti Allahu, Eni ti O fun mi ni ’Ismo‘il ati ’Ishaƙ nigba ti mo ti darugbo. Dajudaju, Oluwa mi ni Olugbo adua

رَبِّ اجْعَلْنِي مُقِيمَ الصَّلَاةِ وَمِن ذُرِّيَّتِي ۚ رَبَّنَا وَتَقَبَّلْ دُعَاءِ(40)

Oluwa mi, se emi ati ninu aromodomo mi ni olukirun. Oluwa wa, ki O si gba adua mi

رَبَّنَا اغْفِرْ لِي وَلِوَالِدَيَّ وَلِلْمُؤْمِنِينَ يَوْمَ يَقُومُ الْحِسَابُ(41)

Oluwa mi, saforijin fun emi ati awon obi mi mejeeji ati awon onigbagbo ododo ni ojo ti isiro-ise yoo sele

وَلَا تَحْسَبَنَّ اللَّهَ غَافِلًا عَمَّا يَعْمَلُ الظَّالِمُونَ ۚ إِنَّمَا يُؤَخِّرُهُمْ لِيَوْمٍ تَشْخَصُ فِيهِ الْأَبْصَارُ(42)

Ma se lero pe Allahu gbagbe nnkan ti awon alabosi n se nise. O kan n lo won lara di ojo kan ti awon oju yoo yo sita rangandan

مُهْطِعِينَ مُقْنِعِي رُءُوسِهِمْ لَا يَرْتَدُّ إِلَيْهِمْ طَرْفُهُمْ ۖ وَأَفْئِدَتُهُمْ هَوَاءٌ(43)

Won yoo ma sare (lo sibi akojo fun isiro-ise), won yoo gbe ori won soke, ipenpeju won ko si nii pada sodo won, awon okan won yo si pa sofo patapata (fun iberu)

وَأَنذِرِ النَّاسَ يَوْمَ يَأْتِيهِمُ الْعَذَابُ فَيَقُولُ الَّذِينَ ظَلَمُوا رَبَّنَا أَخِّرْنَا إِلَىٰ أَجَلٍ قَرِيبٍ نُّجِبْ دَعْوَتَكَ وَنَتَّبِعِ الرُّسُلَ ۗ أَوَلَمْ تَكُونُوا أَقْسَمْتُم مِّن قَبْلُ مَا لَكُم مِّن زَوَالٍ(44)

Kilo fun awon eniyan nipa ojo ti iya yoo de ba won, awon t’o sabosi yo si wi pe: “Oluwa wa, lo wa lara fun asiko die si i, a maa jepe Re, a si maa tele awon Ojise.” Se eyin ko ti bura siwaju pe eyin ko nii kuro nile aye ni

وَسَكَنتُمْ فِي مَسَاكِنِ الَّذِينَ ظَلَمُوا أَنفُسَهُمْ وَتَبَيَّنَ لَكُمْ كَيْفَ فَعَلْنَا بِهِمْ وَضَرَبْنَا لَكُمُ الْأَمْثَالَ(45)

E si gbe ninu ibugbe awon t’o sabosi si emi ara won. O si han si yin bi A ti se pelu won. A tun fun yin ni awon akawe

وَقَدْ مَكَرُوا مَكْرَهُمْ وَعِندَ اللَّهِ مَكْرُهُمْ وَإِن كَانَ مَكْرُهُمْ لِتَزُولَ مِنْهُ الْجِبَالُ(46)

Won kuku ti da ete won, odo Allahu si ni ete won wa, bi o tile je pe (pelu) ete won apata fee le ye lule

فَلَا تَحْسَبَنَّ اللَّهَ مُخْلِفَ وَعْدِهِ رُسُلَهُ ۗ إِنَّ اللَّهَ عَزِيزٌ ذُو انتِقَامٍ(47)

Nitori naa, ma se lero pe Allahu yoo yapa adehun Re ti O se fun awon Ojise Re. Dajudaju Allahu ni Alagbara, Olugbesan

يَوْمَ تُبَدَّلُ الْأَرْضُ غَيْرَ الْأَرْضِ وَالسَّمَاوَاتُ ۖ وَبَرَزُوا لِلَّهِ الْوَاحِدِ الْقَهَّارِ(48)

Ni ojo ti A maa yi ile aye pada si nnkan miiran. (A maa yi) awon sanmo naa (pada. Awon eda) si maa jade (siwaju) Allahu, Okan soso, Olubori

وَتَرَى الْمُجْرِمِينَ يَوْمَئِذٍ مُّقَرَّنِينَ فِي الْأَصْفَادِ(49)

O si maa ri awon elese ni ojo yen, ti won yoo so won papo mora won sinu sekeseke

سَرَابِيلُهُم مِّن قَطِرَانٍ وَتَغْشَىٰ وُجُوهَهُمُ النَّارُ(50)

Oje Ina ni awon ewu won. Ina yo si bo oju won mole bamubamu

لِيَجْزِيَ اللَّهُ كُلَّ نَفْسٍ مَّا كَسَبَتْ ۚ إِنَّ اللَّهَ سَرِيعُ الْحِسَابِ(51)

nitori ki Allahu le san esan ohun ti emi kookan se nise. Dajudaju Allahu ni Oluyara nibi isiro-ise

هَٰذَا بَلَاغٌ لِّلنَّاسِ وَلِيُنذَرُوا بِهِ وَلِيَعْلَمُوا أَنَّمَا هُوَ إِلَٰهٌ وَاحِدٌ وَلِيَذَّكَّرَ أُولُو الْأَلْبَابِ(52)

Eyi ni ise-jije fun awon eniyan nitori ki won le fi se ikilo, ki won si le mo pe (Allahu) Oun nikan ni Olohun ti ijosin to si, Okan soso, ati nitori ki awon onilaakaye le lo iranti


المزيد من السور باللغة اليوربا:

سورة البقرة آل عمران سورة النساء
سورة المائدة سورة يوسف سورة ابراهيم
سورة الحجر سورة الكهف سورة مريم
سورة السجدة سورة يس سورة الدخان
سورة النجم سورة الرحمن سورة الواقعة
سورة الحشر سورة الملك سورة الحاقة

تحميل سورة إبراهيم بصوت أشهر القراء :

قم باختيار القارئ للاستماع و تحميل سورة إبراهيم كاملة بجودة عالية
سورة إبراهيم أحمد العجمي
أحمد العجمي
سورة إبراهيم خالد الجليل
خالد الجليل
سورة إبراهيم سعد الغامدي
سعد الغامدي
سورة إبراهيم سعود الشريم
سعود الشريم
سورة إبراهيم عبد الباسط عبد الصمد
عبد الباسط
سورة إبراهيم عبد الله عواد الجهني
عبد الله الجهني
سورة إبراهيم علي الحذيفي
علي الحذيفي
سورة إبراهيم فارس عباد
فارس عباد
سورة إبراهيم ماهر المعيقلي
ماهر المعيقلي
سورة إبراهيم محمد جبريل
محمد جبريل
سورة إبراهيم محمد صديق المنشاوي
المنشاوي
سورة إبراهيم الحصري
الحصري
سورة إبراهيم العفاسي
مشاري العفاسي
سورة إبراهيم ناصر القطامي
ناصر القطامي
سورة إبراهيم ياسر الدوسري
ياسر الدوسري



Saturday, May 4, 2024

لا تنسنا من دعوة صالحة بظهر الغيب