Taha · 47/135
Itumọ Aṣẹ ohun — Surah Taha
فَأْتِيَاهُ فَقُولَا إِنَّا رَسُولَا رَبِّكَ فَأَرْسِلْ مَعَنَا بَنِي إِسْرَائِيلَ وَلَا تُعَذِّبْهُمْ ۖ قَدْ جِئْنَاكَ بِآيَةٍ مِّن رَّبِّكَ ۖ وَالسَّلَامُ عَلَىٰ مَنِ اتَّبَعَ الْهُدَىٰ ۝٤٧
Faatiyaahu faqoolaaa innaa Rasoolaa Rabbika fa arsil ma`anaa Banee Israaa`eela wa laa tu`azzibhum qad ji`naaka bi Aayatim mir Rabbika wassa laamu `alaa manit taba`al hudaa
📖 Ni Yorùbá
Nitori naa, e lo ba a, ki e so fun un pe: “Dajudaju Ojise Oluwa re ni awa mejeeji. Nitori naa, je ki awon omo ’Isro’il maa ba wa lo. Ma se fiya je won. Dajudaju a ti mu ami kan wa ba o lati odo Oluwa re. Ki alaafia si maa ba eni ti o ba tele imona

🎧 Gbọ


📜 Ẹsẹ 45-49 — Surah Taha

45قَالَا رَبَّنَا إِنَّنَا نَخَافُ أَن يَفْرُطَ عَلَيْنَا أَوْ أَن يَطْغَىٰ
Awon mejeeji so pe: “Oluwa wa, dajudaju awa n paya pe o ma yara je wa niya tabi pe o ma tayo enu-ala.”
46قَالَ لَا تَخَافَا ۖ إِنَّنِي مَعَكُمَا أَسْمَعُ وَأَرَىٰ
(Allahu) so pe: “E ma se paya. Dajudaju Emi wa pelu eyin mejeeji; Mo n gbo (yin), Mo si n ri (yin).”
47فَأْتِيَاهُ فَقُولَا إِنَّا رَسُولَا رَبِّكَ فَأَرْسِلْ مَعَنَا بَنِي إِسْرَائِيلَ وَلَا تُعَذِّبْهُمْ ۖ قَدْ جِئْنَاكَ بِآيَةٍ مِّن رَّبِّكَ ۖ وَالسَّلَامُ عَلَىٰ مَنِ اتَّبَعَ الْهُدَىٰ
Nitori naa, e lo ba a, ki e so fun un pe: “Dajudaju Ojise Oluwa re ni awa mejeeji. Nitori naa, je ki awon omo ’Isro’il maa ba wa lo. Ma se fiya je won. Dajudaju a ti mu ami kan wa ba o lati odo Oluwa re. Ki alaafia si maa ba eni ti o ba tele imona
48إِنَّا قَدْ أُوحِيَ إِلَيْنَا أَنَّ الْعَذَابَ عَلَىٰ مَن كَذَّبَ وَتَوَلَّىٰ
Dajudaju Won ti fi imisi ranse si wa pe dajudaju iya n be fun eni ti o ba pe ododo niro, ti o si keyin si i
49قَالَ فَمَن رَّبُّكُمَا يَا مُوسَىٰ
(Fir‘aon) wi pe: “Ta ni Oluwa eyin mejeeji, Musa?”
TahaAtokọ Kurani
135Ẹsẹ
MeccanRevelation
47Ẹsẹ

Itumọ — Taha 47

Surah Taha Ẹsẹ 47 - Kika, Gbọ, Itumọ, Yorùbá : Nitori naa, e lo ba a, ki e so fun…

Surah Ẹsẹ 47/135 — Surah Taha طه (Meccan). Kika Gbọ Itumọ (Yorùbá). Gbọ: Surah Taha Gbọ, Surah Taha Itumọ, Surah Taha mp3, Surah Taha pdf. Ẹsẹ 45–49. Ni Yorùbá: العربية.




Al-Kur'an


Monday, September 7, 2026

Don't forget us in your sincere prayers