An-Nisa · 110/176
Itumọ Aṣẹ ohun — An-Nisa
وَمَن يَعۡمَلۡ سُوٓءًا أَوۡ يَظۡلِمۡ نَفۡسَهُۥ ثُمَّ يَسۡتَغۡفِرِ ٱللَّهَ يَجِدِ ٱللَّهَ غَفُورًا رَّحِيمًا  ۝١١٠
Wa mai ya`mal sooo`an aw yazlim nafsahoo summa yastaghfiril laaha yajidil laaha Ghafoorar Raheemaa
📖 Ni Yorùbá
Enikeni ti o ba sise aburu kan tabi ti o sabosi si emi ara re, leyin naa ti o toro aforijin lodo Allahu, o maa ba Allahu ni Alaforijin, Alaaanu
🎧 Gbọ

📜 Ẹsẹ 108-112 — An-Nisa

108يَسۡتَخۡفُونَ مِنَ ٱلنَّاسِ وَلَا يَسۡتَخۡفُونَ مِنَ ٱللَّهِ وَهُوَ مَعَهُمۡ إِذۡ يُبَيِّتُونَ مَا لَا يَرۡضَىٰ مِنَ ٱلۡقَوۡلِۚ وَكَانَ ٱللَّهُ بِمَا يَعۡمَلُونَ مُحِيطًا 
Won n fi ara pamo fun awon eniyan, won ko si le fara pamo fun Allahu (nitori pe) O wa pelu won (pelu imo Re) nigba ti won n gbimo ohun ti (Allahu) ko yonu si ninu oro siso. Allahu si n je Alamotan nipa ohun ti won n se nise
109هَٰٓأَنتُمۡ هَٰٓؤُلَآءِ جَٰدَلۡتُمۡ عَنۡهُمۡ فِي ٱلۡحَيَوٰةِ ٱلدُّنۡيَا فَمَن يُجَٰدِلُ ٱللَّهَ عَنۡهُمۡ يَوۡمَ ٱلۡقِيَٰمَةِ أَم مَّن يَكُونُ عَلَيۡهِمۡ وَكِيلًا 
Kiye si i, eyin wonyi ni e n ba won mu awijare wa nile aye. Ta ni o maa ba won mu awijare wa ni odo Allahu ni Ojo Ajinde? Tabi ta ni o maa je alaabo fun won
110وَمَن يَعۡمَلۡ سُوٓءًا أَوۡ يَظۡلِمۡ نَفۡسَهُۥ ثُمَّ يَسۡتَغۡفِرِ ٱللَّهَ يَجِدِ ٱللَّهَ غَفُورًا رَّحِيمًا 
Enikeni ti o ba sise aburu kan tabi ti o sabosi si emi ara re, leyin naa ti o toro aforijin lodo Allahu, o maa ba Allahu ni Alaforijin, Alaaanu
111وَمَن يَكۡسِبۡ إِثۡمًا فَإِنَّمَا يَكۡسِبُهُۥ عَلَىٰ نَفۡسِهِۦۚ وَكَانَ ٱللَّهُ عَلِيمًا حَكِيمًا 
Enikeni ti o ba da ese kan, o da a fun emi ara re. Allahu si n je Onimo, Ologbon
112وَمَن يَكۡسِبۡ خَطِيٓـَٔةً أَوۡ إِثۡمًا ثُمَّ يَرۡمِ بِهِۦ بَرِيٓـًٔا فَقَدِ ٱحۡتَمَلَ بُهۡتَٰنًا وَإِثۡمًا مُّبِينًا 
Enikeni ti o ba se asise kan tabi ese kan, leyin naa, o di i ru alaimowo-mese, o ti da oran iparomoni ati ese ponnbele
An-NisaAtokọ Kurani
176Ẹsẹ
MedinanRevelation
110Ẹsẹ

Itumọ — An-Nisa 110

Surah Ẹsẹ 110/176 — An-Nisa النساء (Medinan). Kika Gbọ Itumọ (Yorùbá). Gbọ: An-Nisa Gbọ, An-Nisa Itumọ, An-Nisa mp3, An-Nisa pdf. Ẹsẹ 108–112. Ni Yorùbá: العربية.




Al-Kur'an


Tuesday, August 18, 2026

Don't forget us in your sincere prayers