An-Nisa · 118/176
Itumọ Aṣẹ ohun — An-Nisa
لَّعَنَهُ اللَّهُ ۘ وَقَالَ لَأَتَّخِذَنَّ مِنْ عِبَادِكَ نَصِيبًا مَّفْرُوضًا ۝١١٨
La`anahul laah; wa qaala la attakhizanna min `ibaadika naseebam mafroodaa
📖 Ni Yorùbá
Allahu sebi le Esu. O si wi pe: "Dajudaju mo maa mu ipin ti won pin fun mi ninu awon erusin Re
🎧 Gbọ

📜 Ẹsẹ 116-120 — An-Nisa

116إِنَّ اللَّهَ لَا يَغْفِرُ أَن يُشْرَكَ بِهِ وَيَغْفِرُ مَا دُونَ ذَٰلِكَ لِمَن يَشَاءُ ۚ وَمَن يُشْرِكْ بِاللَّهِ فَقَدْ ضَلَّ ضَلَالًا بَعِيدًا
Dajudaju Allahu ko nii forijin (eni ti) o ba n sebo si I. O si maa saforijin fun ese miiran yato si iyen fun eni ti O ba fe. Enikeni ti o ba n sebo si Allahu, dajudaju o ti sina ni isina t’o jinna
117إِن يَدْعُونَ مِن دُونِهِ إِلَّا إِنَاثًا وَإِن يَدْعُونَ إِلَّا شَيْطَانًا مَّرِيدًا
Won ko pe kini kan leyin Allahu bi ko se awon abo orisa. Won ko si pe kini kan bi ko se Esu oluyapa
118لَّعَنَهُ اللَّهُ ۘ وَقَالَ لَأَتَّخِذَنَّ مِنْ عِبَادِكَ نَصِيبًا مَّفْرُوضًا
Allahu sebi le Esu. O si wi pe: "Dajudaju mo maa mu ipin ti won pin fun mi ninu awon erusin Re
119وَلَأُضِلَّنَّهُمْ وَلَأُمَنِّيَنَّهُمْ وَلَآمُرَنَّهُمْ فَلَيُبَتِّكُنَّ آذَانَ الْأَنْعَامِ وَلَآمُرَنَّهُمْ فَلَيُغَيِّرُنَّ خَلْقَ اللَّهِ ۚ وَمَن يَتَّخِذِ الشَّيْطَانَ وَلِيًّا مِّن دُونِ اللَّهِ فَقَدْ خَسِرَ خُسْرَانًا مُّبِينًا
Dajudaju mo maa si won lona. Mo maa fi erokero sinu okan won. Mo maa pa won lase, won yo si maa ge eti eran-osin (lati ya a soto fun orisa). Mo maa pa won lase, won yo si maa yi eda Allahu pada." Enikeni ti o ba mu Esu ni ore leyin Allahu, dajudaju o ti sofo ni ofo ponnbele
120يَعِدُهُمْ وَيُمَنِّيهِمْ ۖ وَمَا يَعِدُهُمُ الشَّيْطَانُ إِلَّا غُرُورًا
Esu n sadehun fun won, o si n fi ife-iro sinu okan won. Esu ko si sadehun kan fun won bi ko se etan
An-NisaAtokọ Kurani
176Ẹsẹ
MedinanRevelation
118Ẹsẹ

Itumọ — An-Nisa 118

Surah An-Nisa Ẹsẹ 118 - Kika, Gbọ, Itumọ, Yorùbá : Allahu sebi le Esu. O si wi pe: "Dajudaju mo…

Surah Ẹsẹ 118/176 — An-Nisa النساء (Medinan). Kika Gbọ Itumọ (Yorùbá). Gbọ: An-Nisa Gbọ, An-Nisa Itumọ, An-Nisa mp3, An-Nisa pdf. Ẹsẹ 116–120. Ni Yorùbá: العربية.




Al-Kur'an


Tuesday, August 18, 2026

Don't forget us in your sincere prayers